BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìjọba yóò máa gba ìwé ìrìnnà lọ́wọ́ àwọn tó bá ní àwọn kì í ṣe ọmọ Naijiria mọ́
Atẹjade naa ṣalaye pe awọn eeyan ti Aarẹ ba ti gba pe awọn ki i ṣe ọmọ Naijiria mọ ni ọrọ yii kan.
Àwọn agbẹ́bọn tún pa ọ̀dọ́ l'Ondo, aráàlú fi ẹ̀hónú hàn
Lati le fopin si ikọlu ati ijinigbe tó n waye lemọlemọ naa, ati lati kesi ijọba fun ojutuu lo jẹ kawọn olugbe agbegbe yii gbegi di opopona to lọ si ofiisi Gomina, niluu Akure, lati fi ehonu han.
Ìjọba Nàìjíríà kéde orúkọ àwọn afurasí tó ń ran ìgbésùnmọ̀mí lọ́wọ́
Igbimọ 'Nigeria Sanctions Committee' (NSC) to gbe awọn orukọ naa jade ko sọ ọmọ orilẹede ti wọn jẹ, bẹẹ ni ko ṣalaye bi ipa ti wọn ti ko ninu igbesunmọmi ṣe pọ to.
Póòpù ń ṣàbẹ̀wò sílẹ̀ Africa pẹ̀lú ìwáásù àlááfíà àti ìṣọ̀kan
Àbẹ̀wò Pope Leo XIV sílẹ̀ Africa yìí ló máa jẹ́ ìrìnàjò rẹ̀ tó gùn jùlọ láti ìgbà tó ti di póòpù ìjọ Àgùdà.
Fídíò, Kí ló sọ àwọn ológbò di gbajúmọ̀ orí ayélujára ní Instabul?, Duration 1,25
Níṣe ni àwọn ológbò ti di gbajúmọ̀ lórí ayélujára báyìí bí ọ̀pọ̀ àwọn èèyàn tó ń rìnrìnàjò afẹ́ lọ sí Instabul ṣe ń tò láti bá àwọn ológbò yàwòrán.
Fídíò, Àwọn òṣèré òde òní nílò láti máa ṣàgbéyẹ̀wò ìtàn tí wọ́n ń kọ, a kìí ṣe eégún oníhòhò - Lere Paimo, Duration 4,12
Nínú ìfọ̀rọ̀wérọ̀ tí àgbà òṣèré Lere Paimo ṣe pẹ̀lú BBC News Yorùbá ló ti ṣàlàyé bí ìrìnàjò sínú eré tíátà ṣe bẹ̀rẹ̀ àti ibi tó dé dúró lónìí.
Fídíò, Arọ́bafin ni Sẹ́nétọ̀ Adeseun ni mo fi ní kó gáfárà fún ipò Mayegun ìlú Ogbomoso – Soun Ghandi Laoye, Duration 3,55
Ọbalaye naa ni Sẹnetọ Adeṣeun ko fi arinfin rẹ fun Ṣọun bo rara, koda o tun sọrọ alufansa sii ni gbangba.
Àwọn agbébọn tún ya bo ìjọba ìbílẹ̀ Kaiama ní Kwara, ṣekúpa ẹ̀ṣọ́ asọ́gbó márùn ún, dáná sun ọkọ̀ àti alùpùpù
Eyi ko ṣẹyin bi awọn agbebọn ṣe kọlu ilu naa ni nnkan bii aago mẹta owurọ oni, ọjọ kẹwaa, oṣu Kẹrin, ọdun 2026 ti wọn si ṣekupa awọn ẹṣọ asọgbo marun-un.
Ìdílé oyè fún Gómìnà Adeleke ní gbèdéke ọjọ́ méje láti rọ Apetumodu tó ń ṣẹ̀wọ̀n l'Ámẹ́ríkà lóyè
Ile ẹjọ kan lorilẹede Amẹrika lo dajọ ẹwọn fun Ọba Apetumodu ti ilu Ipetumodu ti wọn ni o jẹbi ẹsun lilu jibiti pẹlu eto ẹyawo COVID-19 ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ fun awọn okoowo kekeke to fara kaasa lasiko ajakalẹ arun naa.
Ìjọba àpapọ̀ ké gbàjarè lẹ́yìn tí àrùn tó ń gbẹ̀mí màlúù kọlu ìpínlẹ̀ 17
Ijọba ni arun naa n ṣakoba fun ọrọ aje ohun ọsin ati pe ti ijọba ko ba tete kapa rẹ, o le pa odidi agbo maluu kan run.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,01
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ aláàbò ilẹ̀ Ibadan tuntun, Ibadan Community Guard
Aafin Olubadan to wa ni Oke Aremo niluu Ibadan ni wọn ti ṣe eto naa.
Akẹ́kọ̀ọ́ Covenant University jáde láyé níbi tó ti ń gbá bọ́ọ̀lù, Ilé ẹ̀kọ́ ṣàlàyé ohun tó fa ikú rẹ̀
Ìròyìn tó gba orí ayélujára ni pé lásìkò tí akẹ́kọ̀ọ́ náà ń kópa nínú bọ́ọ̀lù àfẹsẹ̀gbá ló déédé ṣubú lulẹ̀, tí kò sì tètè rí ìtọ́jú tó fi gba ibẹ̀ jáde láyé.
Amẹ́ríkà gbé ìkìlọ̀ tuntun jáde lórí ọ̀rọ̀ àbò ní Nàìjíríà, Ó ní ìlú Abuja àtàwọn ìpínlẹ̀ 23 kan ti di ibi àìgbọdọ̀ wọ̀ fáwọn èèyàn rẹ̀, ìdí rèé
Ni irọlẹ Ọjọru ọjọ kẹjọ oṣu Kẹrin ọdun yii ni ileeṣẹ ijọba Amẹrika to n ri si ọrọ ilẹ okeere fi ikilọ naa sita.
Ẹ múra o! Òjò ńlá tó le fa àgbárá òjò ń bọ̀ ní ìpínlẹ̀ mẹ́wàá - NiMet
Ninu atẹjade ti ajọ naa fi sita lọjọru ni wọn ti tun sọ pe iji yoo waye lawọn ipinlẹ kan nigba ti oorun yoo si jade lawọn ibomiran.
Àlàyé lórí ohun tó fa rògbòdìyàn inú ẹgbẹ́ ADC, èyí tó jẹ́ kí INEC yẹ àga máwọn adarí ẹgbẹ́ náà nídìí
Awuyewuye lori igbimọ adari ẹgbẹ oṣelu ADC bẹrẹ loṣu Keje ọdun 2025 nigba tawọn adari ẹgbẹ naa kọwe fipo silẹ ti David Mark si di alaga fidihẹ.
Ṣé lóòótọ́ làwọn ọmọ ogun máa ń ra aṣọ ogun àti ohun ààbò fúnra wọn?- iléeṣẹ́ ológun sọ̀rọ̀
Àtẹ̀jáde kan tí adelé adarí ẹ̀ka tó ń rí sí ọ̀rọ̀ aráàlú ní iléeṣẹ́ ológun Nàìjíríà, Appolonia Anele fi léde lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun sọ pé irọ́ tó jìnà sí òótọ́ ni ẹ̀sùn náà àti pé ó le ṣi ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́kàn.
Wáyà iná ẹ̀lẹ́ńtíríkì já, iná ṣẹ́yọ, ṣekúpa èèyàn kan ní Ilọrin, ọ̀pọ̀ farapa, dúkìá olówó iyebíye jó mọ́lé
Àwọn èèyàn agbègbè náà ní ibi tí wọ́n ti ń gbìyànjú láti yọ ohun èlò kúrò lára iná ló ti gbé e.
Mi ò bá Makinde àti Olubadan jà, ìdí rèé táwọn èèyàn kò fi rí mi pọ̀ mọ́ Gómìnà àti Ọba Ladoja - Alaafin
Alaafin ni oun ni ibaṣepọ to dan mọran pẹlu Ọba Rashidi Ladoja ati Gomina ipinlẹ Oyo.
Wo àwọn ojú pópó tí yóò wà ní títì pa nílùú Eko lásìkò àbẹ̀wò Tinubu bẹ̀rẹ̀ láti òní
Kọmiṣọna fun igbokegbodo ọkọ nipinlẹ Eko, Oluwaseun Osiyemi, sọ ninu atẹjade kan to fi sita pe igbesẹ yii waye lati le jẹ ki eto ifilọlẹ awọn akanṣẹ iṣẹ ti Gomina Babajide Sanwo-Olu ti aarẹ fẹ ṣe lọ ni irọwọ rọsẹ.
Àwọn afurasí darandaran ṣá àgbẹ̀ sínú oko rẹ̀ l'Ogbomoso lẹ́yìn tó ní wọn kò gbọdọ̀ da ẹran níbẹ̀
Awọn afurasi darandaran naa ni wọn fẹ fi awọn maalu wọn jẹ oko oloogbe Kehinde lọjọ Isinmi, ọjọ karun un, oṣu Kẹrin ọdun 2026 yii, amọ o kọ jale ki wọn to gbẹmi rẹ.
Mílíọ́nù méjìdínlógójì tọ́ọ̀nù oúnjẹ ló ń ṣòfò ní Naijiria lọ́dọdún – Àjọ EU
Wọn ni ti ounjẹ ba n ṣofo, o n tumọ si pe omi, asiko ati okun ti wọn fi pese ounjẹ naa ti ṣofo niyẹn.
Àwọn dókítà ṣẹ́wélé ìyanṣẹ́lódì, fún ìjọba ní gbèdéke
Iwadii fi han wi pe awọn dokita nile iwosan ijọba ti daṣẹ silẹ fun ọjọ mọkanlelaadọta lati igba ti ijọba Aarẹ Bola Tinubu ti bẹrẹ.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Kí ni yóò ṣẹlẹ̀ tí gbèdéke tí Trump fún Iran lórí 'Strait of Hormuz' bá kọjá?
Ó ní láti dènà irúfẹ́ ìkọlù yìí, Iran gbọdọ̀ gbà àwọn nǹkan tí òun ń fẹ́, tó fi mọ́ fífi ààyè gba gbígbé epo láì sí ìdàmú gba Strait of Hormuz.
Wo orílẹ̀èdè márùn-ún tí inú àwọn èèyàn rẹ̀ dùn jùlọ lágbàáyé lọ́dún 2026
Ìjábọ̀ náà, tí àjọ Oxford Health Research Institute pẹ̀lú àjọṣepọ̀ United Nations Sustainable Development Goals máa ń gbé jáde ní ọdọọdún, máa ń ṣe àgbéyẹ̀wò ètò ọrọ̀ ajé, àtìlẹyìn àwùjọ, bí àwọn èèyàn ṣe ní àǹfàní láti lè jáde bó bá ṣe wù wọ́n sí, àti bí ẹ̀mí àwọn èèyàn ṣe le gùn sí ní orílẹ̀ èdè ogóje (140) káàkiri àgbáyé yẹ̀wò.
A ti dóòlà èèyàn 31 tí wọ́n jí gbé nílé ìjọsìn lọ́jọ́ ọdún Àjínde – Ilésṣẹ́ ọmọ ogun
Bo tilẹ jẹ pe ileeṣẹ ọmọ ogun sọ pe awọn ko fi akoko ṣofo ki awọn to ya bo ile ijọsin ti ikọlu naa ti waye, awọn to wa nibẹ sọ fun awọn akọroyin pe fun ọpọ wakati lawọn agbesunmọmi naa fi ṣọṣẹ lai si idwọ kankan.
Àṣìta ìbọn ṣekúpa ọ̀dọ́binrin ọmọ ọdún mẹ́rìnlá nínú ilé, ìwádìí bẹ̀rẹ̀
Ileeṣẹ ologun ni iwa aibikita ni awọn to yinbọn naa hu, ati pe ileeṣẹ ologun ti bẹrẹ iwadii lati mọ awọn to yinbọn to pa ọmọdebinrin naa.
Ìmọ̀ ìjìnlẹ̀ sáyẹ́nsì ṣo ohun tó pa Jesu
Ẹya Jew ni Jesu, o dari awọn to tẹle e, ṣugbọn iṣesi rẹ ko tẹ awọn alaṣẹ ilẹ Rome lọrun.
Àwọn èèyàn Burkina Faso gbọdọ̀ gbàgbé nípa ìjọba awarawa – Ibrahim Traoré
Ṣaaju ni Traoré ti kọkọ ṣeleri lati da ijọba pada fun awọn oloṣelu ninu oṣu Keje ọdun 2024 amọ nigba to ku oṣu meji ki gbedeke to da pe, o kede pe awọn ologun ni yoo ṣi maa tukọ ilẹ naa lọ fun ọdun marun un mii.
Ìjọba àpapọ̀ yóò san gbèsè ₦3.3trn owó iná tó jẹ láti ọdun 2015
Yatọ si sisan gbese yii, Onanuga fi kun pe awọn iṣẹ mii ṣi n bọ lọna, bii eto mita ti yoo jẹ ki araalu maa san owo fun ina ti wọn ba lo nika ṣoṣo.
Àlàyé lórí bí Amẹrika ṣe dóòlà ọmogun rẹ̀ tó wà nínú bàálù ìjagun tí Iran fi àdó olóró já lulẹ̀
Awọn ọmogun Amẹrika mejeeji ti wọn wa ninu baalu naa lo raye jade lẹyin ti Iran yin ado oloro si baalu ijagun naa.
Eré Àjíǹde di wàhálà! Akẹ́kọ̀ọ́ dèrò ilé ìwòsàn lẹ́yìn tí wọ́n lú ú bí bàrà lásìkò tó ṣe Jesu nínú eré Ajinde
Ìròyìn ní ọ̀rọ̀ bẹ́yìn yọ nígbà tí wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí ní lu Dennis láti ṣàfihàn àwọn ìyà tí Jésù jẹ nígbà ayé rẹ̀ èyí tó mú kí wọ́n lù ú bí ẹni lu bàrà, tó sì tara bẹ́ẹ̀ farapa gidigidi.
"Blessing CEO, dá ₦20m ti mo fun ọ lórí àrùn jẹjẹrẹ tí o sọ pé ó ń ṣe ọ́ padà" Oil Money yarí, Blessing náà fèsì
Oil Money sọ pe ogun miliọnu loun fun Blessing, o si gbọdọ da a pada bayii laaarin ọjọ meje.
Àlàyé rèé lórí ohun tó ṣokùnfà ikú Destiny Boy
Lọjọ kẹtadinlogun oṣu Kinni ọdun 2026 yii ni ọdọmọde olorin naa ku lojiji lẹni ọdun mejilelogun.













































































