BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Adeleke wọ́ báǹkì First Bank àti EFCC lọ sílé-ẹjọ́ lórí àkáǹtì ìjọba Osun tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé
Ajọ EFCC lo gbẹsẹ le apo aṣuwọn ikowosi ijọba ipinlẹ Osun l'Ọjọru, ọsẹ yii, nibi ti wọn ti sọ pe awọn ṣakiyesi ọpọ owo to n fo kaakiri lati inu apo ikowosi naa lọ apo aṣuwọn miran to jẹ ti awọn ileeṣẹ aladani.
Fídíò, Ìpínlẹ̀ Osun kò nílò ẹ̀jẹ̀ ẹnikẹ́ni láti tẹ̀ síwájú, ẹ̀yin olóṣèlú tó ń pa èèyàn, ẹ jáwọ́ níbẹ̀ – Olùdíje gómìnà ZLP, Duration 3,33
BBC News Yoruba ba oludije sipo gomina fun ẹgbẹ oselu Zenith Labour Party, ZLP, Enginia Olufemi Adesuyi sọrọ lati mọ ọpọ ohun to fẹ se fun araalu.
Mo bẹ gómìnà Imo láti gba àláàfíà láàyè lásìkò ìbò gómìnà l‘Osun, kó sì rántí pé ọmọ ìpínlẹ̀ Imo ni aya mi - Davido
Davido parọwa yii lasiko ipade awọn akọroyin to se nilu Osogbo ni ọjọru, o sọ nipa idi to se yẹ ki gbogbo awọn olugbe ipinlẹ naa gba alaafia laaye saaju, lasiko ati lẹyin idibo naa.
Wó kókó méjìlá tó yẹ kí o mọ̀ nípa Temitope Osoba, òṣèré tíátà tó jáde láyé
Lara awọn adojukọ ojiji ti oṣerebinrin naa koju ni ti aisan jẹjẹrẹ ọmu to kọluu lọsan gangan.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 1,01
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́
Kí ló dé tí obìnrin kan ṣe bẹ́ sínú Ọ̀sà l‘Eko, kí àwọn òmùwẹ̀ apẹja tó dóòlà ẹ̀mí rẹ̀?
Awọn to wa nibẹ lasiko iṣẹlẹ naa sọ pe ile aye lo su obinrin ọhun, to fi pinnu lati gba ẹmi ara rẹ lojiji.
Fídíò, "Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́", Duration 4,47
Eniola ko le da rin, ko le da jokoo, ko le da sun, ko le da yagbẹ, bẹẹ tun ni ko le da tọ funra rẹ. Awọn nnkan wọnyi lo si maa n ko ironu ba a lojoojumọ, paapaa nigba to ba n ranti awọn afojusun rẹ lati kekere.
Wo ọgbọ́n àlùmọ̀kọ́rọ́yí tuntun márùn-ún táwọn agbésùnmọ̀mí ń lò láti ṣe ìkọlù apanirun
BBC ṣayẹwo awọn ọgbọn alumọkọrọyi marun-un tawọn ikọ apani n lo bayii lati fi ṣe ikọlu apanirun, bí wọn ko ṣe fi ikọlu yii mọ lori araalu lasan mọ.
Idà ahun ti pa ahun! Àdó olóró bú, pa ọ̀pọ̀ ọmọ ẹgbẹ́ ISWAP lásìkò tí wọn n to àdó ikú papọ̀ láti kọlu iléeṣẹ́ ológun
Iroyin ni ado oloro ti wọn fẹ lọ fi ṣọṣẹ lagbegbe kan nibẹ lo bu gbamu lasiko ti wọn ko tii ṣetan fun ikọlu ti wọn n lọ ṣe.
Lẹ́yìn oṣù mẹ́fà nígbèkùn, àwọn tí agbésùnmọ̀mí gbé lọ nílùú Woro àti Nuku ní Kwara gba ìtúsílẹ̀
Loju opo Facebook to jẹ ti ijọba ipinlẹ Kwara ni wọn ti kede itusilẹ ọhun l'Ọjọru, ọjọ karun-un oṣu Kẹjọ ọdun 2026. Ijọba ibilẹ Kaiama ni ilu Woro ati Nu
"Ìyá àgbà dá abẹ́ fún ọmọ mi obìnrin láìjẹ́ kí n mọ̀ nípa rẹ̀, torí pé àwọn ọkùnrin máa ń fi obìnrin tí kò bá dá abẹ́ ṣe yẹ̀yẹ́"
Gẹgẹ bi José Carlos Cueto ṣe gbe e jade, nigba ti wọn gbe aba naa sita nile aṣofin Colombia, ọpọ ariyanjiyan lo waye fifi opin si ohun ti wọn lo lewu pupọ naa.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ilé tí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ń gbé dàwó, èèyàn méjì kú, mẹ́ta dèrò ilé ìwòsàn
Akojọpọ awọn adoola ẹmi lati ajọ Red Cross, NEMA, ileeṣẹ adoola ẹmi ipinlẹ Anambra, SEMA, ileesẹ panapa, ileeṣẹ ọlọpaa atawọn adoola ẹmi miran ni wọn wa nibẹ.
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
Ṣaaju asiko yii ni Kabiesi Olubadan, Ọba Rashidi Adewolu Ladoja ti kọkọ kede ninu atẹjade kan pe ki awọn araalu, paapaa awọn obinrin, ṣora fun Egungun naa.
Mo gbọ́ pé àwọn kan láwọn fẹ́ jíbò l'Osun, eré ọmọdé ni, ìbò Osun ò ṣe é fọwọ́ kàn – Gómìnà Adeleke
Oke Ila ni Gomina Adeleke ti sọrọ naa, nijọba ibilẹ Ifedayo, ipinlẹ Osun, lasiko iwọde ipolongo ibo to ku si dẹdẹ naa.
Àlàyé rèé lórí bọ́wọ́ ṣe tẹ afurasí sọ́jà tó ń ta aṣọ ọmọ ogun Naijiria fún áwọn agbésùnmọ̀mí
Afurasi naa, Mohammed Yusuf pẹlu nọmba 23NA/84/1939 Private to n ṣiṣẹ pẹlu ẹka ileeṣẹ ologun to n ran aṣọ awọn ọmogun niluu Eko ni wọn mu ni nnkan bii ago mẹfa aabọ lopin ọsẹ to kọja lẹyin iṣẹ iwadii kan ti ileeṣẹ ologun ṣe.
Ọmọ Nàìjíríà míràn tún kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá ní South Africa; Ìjọba Nàìjíríà fárígá, pè fún ìwádìí kíkún
Tẹ o ba gbagbe, South Africa ti n le awọn ajeji rẹpẹtẹ kuro nilẹ naa o ti pẹ, paapaa awọn alawọ dudu ti wọn jẹ ọmọ Africa bii tiwọn, lori ẹsun pe wọn ko je kawọn riṣẹ ṣe niluu abinibi awọn.
Tinubu àti Atiku tún gbéná wojú ara wọn lórí ìgbẹ́jọ́ Tinubu tí iléeṣẹ́ kan gbé dìde ní Amẹ́ríkà
Awuyewuye to n waye lasiko yii laaarin awọn mejeeji ko ṣẹyin bi ileeṣẹ aarẹ ṣe fẹsun kan Atiku pe o n ṣe agbatẹru ileeṣẹ kan ni Amẹrika lati lọ ṣagbedide iwadii lori igbẹjọ ti Tinubu koju ni Amẹrika lọdun 1993.
A kò tí ì fún PFIPC ní kọ́bọ̀ nínú ₦1.3bn tí wọ́n yà sọ́tọ̀ fún un - Ọ́fíìsì ètò ìṣúná
Ọjọ Ẹti, ọjọ kẹrindinlọgbọn oṣu Keje ọdun 2026 yii ni Adari pata nileeṣẹ ijọba naa, Tanimu Yakubu, yọju si igbimọ to n tọpinpin N1.3 billion to wa ninu iṣuna ọdun 2026 fun ileeṣẹ PFIPC.
Àwọn olùgbé Akure pariwo lórí òórùn tó gbalẹ̀ kan, ìjọba bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
Ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Ondo to n ri ọrọ ayika ti fidi rẹ mulẹ pe iwadii ti fi han pe oorun yii ko ṣẹyin awọn eeyan kan ti wọn n da idọti lọna aitọ sina odo to n ṣan.
Olórí àwọn tó ń pèsè owó fún ẹgbẹ agbésùnmọ̀mí ISWAP ní Naijiria jọ̀wọ́ ara rẹ̀ fún ọmọ ogun
Ninu atẹjade kan, ileeṣẹ ọmọ ogun sọ pe igbesẹ afurasi naa lo n waye lasiko ti pupọ awọn agbesunmọmi bi tirẹ bẹrẹ si n jọwọ ara wọn fun ileeṣẹ ọmọ ogun.
Ẹ wo ilé ìwòsàn táwọn aláboyún ti ń bímọ sórí ẹní
Ile iwosan alabọde Badawa ti dẹnu kọlẹ lati bi ọdun mẹwaa ti atẹgun ojo ti ba apa kan ile iwosan naa jẹ.
America kìlọ̀ fáwọn ọmọ Nàìjíríà tó tún jẹ́ ọmọ America láti má ṣe lo ìwé ìrìnná míràn yàtọ̀ sí ti orílẹ̀èdè náà láti wọlé tábì jáde l'America
Ninu atẹjade kan ti ajọ naa fi lede loju opo X rẹ lọjọ Aiku, ni wọn ti kede pe eyi kan gbogbo ọmọ oniluu l'America pẹlu, titi kan awọn ọmọde to ba ti jẹ ọmọ oniluu meji.
Kókó ohun tó wà nínú owó oṣù tuntun fáwọn ológun tí Ààrẹ Tinubu buwọ́lu
Afikun owo oṣu naa wa laaarin ida ọgbọn si ọgọrin (30-80%) gẹgẹ bi Oludamọran pataki fun aarẹ lori eto iroyin, Bayo Onanuga, ṣe fi lede lọjọ Iṣẹgun.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Adeleke pàṣẹ kí àtúnṣe bẹ̀rẹ̀ lórí afárá tó bẹ̀rẹ̀ sí ń yẹ̀ lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ mẹ́ta tí wọ́n ṣi nílùú Osogbo
Ọjọ kinni, oṣu Keje, ọdun 2026 yii ni wọn ṣi afara naa amọ o ṣeni laanu pe ko tii to ọsẹ mẹta pere ti wọn ṣi ti apakan rẹ bẹrẹ si n jin wọnu lẹyin ojo arọrọda kan.
Wo àwọn adarí ẹgbẹ́ NURTW tí wọ́n ti gbẹ̀mí wọn nílùú Eko
Eyii ni akojọpọ awọn kan lara awọn adari NURTW ti wọn ti ṣekua niluu Eko.
Àlàyé rèé lórí bí eégún Olóòlù ṣe dé Ibadan, ìdí tí kìí fi wọ bàtà tàbí fojú kan obìnrin
Ní kété tí ènìyàn bá ti dárúkọ eégún Oloolu ní Ibadan, kálukú yoo máa forí gbárí, torí ẹ̀rù àti agbára tó wà lára rẹ̀
Kí ló dé tí orin K1 "Tó bá lóyún kóyún, sàárà ni" fi ń mi orí ayélujára tìtì? Àlàyé rèé
Arabinrin toun ni oun bimọ fun K1 sọ pe oun lọ ba mama K1 lori ọrọ ọmọ oun Azizat, mama si ṣe bi abiamọ nigba ti wọn ri ọmọ naa.
Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa
Ti ẹ o ba gbagbe, ọjọ Aiku akọkọ oṣu kẹfa ọdun yii ni awọn agbebon ọhun sẹkupa Ọgbẹni Olaleye, gẹgẹ bi giwa ile ẹkọ girama, Ahoro Esinele, iyẹn, Arabinrin Rachael Alamu ṣe fi idi rẹ mulẹ.
Ìbanilórúkọjẹ́ lẹ̀sùn ìkówójẹ tí wọ́n fi kàn mí, Oluomo sọ̀rọ̀ lẹ́yìn tílé aṣòfin Ogun fagilé ẹ̀sùn tí wọ́n fi kan adarí ilé tẹ́lẹ̀
Ile tun fẹnuko nibi ijokoo wọn lonii Ọjọru niluu Abeokuta wi pe iyọnipo rẹ ti di ikọwefiposilẹ bayii.
Mi ò lérò pé mo lè dé ipò Ìmáàmù ìlú Ilorin, àmọ́, mo ti máa ń rí àwọn àpẹẹrẹ kan tipẹ́ - Ìmáàmù Ilorin tuntun
Imaamu Ilorin tuntun fikun ọrọ rẹ pe awọn musulumi ko gbọdọ jẹ ki ero awọn ọta Islam to maa n sọ pe ẹsin jagidijagan ni ẹsin Islam ṣẹ mọ wọn wa lara.
Ọlọ́pàá mẹ́rin tó bèèrè owó ẹ̀yìn lọ́wọ́ awakọ̀ lọ́nà márosẹ̀ Ọrẹ si Benin wọ gàù, ilé-iṣẹ́ ọlọ́pàá bẹ̀rẹ̀ ìwádìí lórí wọn
Gẹgẹ bi kọmandi ọlọpaa Ondo ṣe wi loju opo X, wọn ti mọ awọn ọlọpaa to wa ninu fidio yii, iwadii ati igbesẹ to yẹ si ti bẹrẹ lorii wọn.
Kókó ìpàdé Sẹ́nẹ́tọ̀ Folarin pẹ̀lú Ààrẹ Tinubu lórí awuyewuye nípa olùdíje sípò gómìnà fẹ́gbẹ́ APC ní ìpínlẹ̀ Oyo
Ipade naa ni wọn lo da lori erongba lati fi opin si gbogbo aawọ, wahala ati ikunsinu to wa laaarin awọn agbaagba ati alẹnulọrọ ẹgbẹ APC nipinlẹ Oyo, ṣaaju eto idibo gomina to fẹẹ waye ninu oṣu Keji, ọdun 2027.
Mo Bimpe lérí láti gbé àwọn tó ní Lateef Adedimeji kọ́ ni bàbá àwọn ọmọ rẹ̀ lọ sílé ẹjọ́
Lori ayelujara ni iroyin to ni Lateef Adedimeji kọ ni baba awọn Ibẹta ti n tan kalẹ
Fọ́nrán bí Abacha ṣe kú wà lọ́wọ́ mi, arúmọjẹ lásán ni ìtàn táwọn kan ń kọ sínú ìwé kiri - Al-Mustapha, olórí ẹ̀ṣọ́ aláàbò fún Abacha
Latigba ti iku Ọgagun Abacha ti jade sita, ni ariyanjiyan ti wa kaakiri agbaye, paapaa nilẹ Naijiria to ti jẹ adari, ti awọn eeyan ko si gbagbe titi di asiko yii.
Kílódé tí àwọn èèyàn ń fi ohùn ránṣẹ́ sí Gheghe lórí ayélujára?
Gheghe gbajumọ fun awọn ọrọ to maa n sọ lori ayelujra fun awọn ọkunrin lori bi wọn ko sẹ gbọdọ maa na owo wọn fun obinrin.















































































