BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Wo àwòrán Ọmọọba Harry àti Ìyàwó rẹ̀ nígbà tí wọ́n dé sí Naijiria
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry pẹlu Iyawo rẹ lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Naijiria
Published
11 Èbibi 2024
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n ya fọtọ pẹlu Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan, ti wọn si n ki wọn kaabọ
Àkọlé àwòrán,
Wọn fi ilẹkẹ da Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan lọla lati bu ọwọ fun wọn gẹgẹ bii eeyan nla
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Kanduna, Uba Sani ati Ọmọọba Harry nigba to ba lẹ si ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tun fi aṣọ agbada nla da lọla.
Àkọlé àwòrán,
Awọn onijo ibilẹ fi ijo da Ọmọọba ati iyawo rẹ lara ya lasiko abẹwo.
Àkọlé àwòrán,
Gomina Uba Sani ati Ọmọọba Harry ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry ati Gomina ipinlẹ Kaduna n wo bi awọn onijo ṣe n fi ijo da wọn lara ya ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Awọn onilu ni ile ijọba
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ibilẹ n fi orin da Ọmọọba lọla.
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
03:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration3,22
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration2,34
02:21
Fídíò,
Olaniyan 'Idamu Industry' Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò 'Ṣé o láyà?'
, Duration2,21
05:24
Fídíò,
Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
, Duration5,24
01:40
Fídíò,
Wo bí hòmóònù ṣe ń mú àyípadà bá ìhùwàsí àwọn obìnrin ní ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀
, Duration1,40
04:05
Fídíò,
Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú - Abayomi Alvin
, Duration4,05
01:02
Fídíò,
Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà
, Duration1,02
05:59
Fídíò,
Ṣọ́ọ̀ṣì kan rèé tí wọn kií lanu sọ̀rọ̀, ọwọ́ lásán làwọn akọrin, oníwàásù àti olùjọ́sìn fi ń júwe
, Duration5,59
00:52
Fídíò,
Àwọn aṣọ aláràmbarà tí wọ́n lò níbi ayẹyẹ AMVCA
, Duration0,52
03:29
Fídíò,
"Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé"
, Duration3,29
01:30
Fídíò,
"Iṣẹ́ tóo yàn láàyò lè ṣàkóbá fún ìlera ọpọlọ rẹ lọ́jọ́ alẹ́"
, Duration1,30
Ìròyìn tó ṣe kókó
Olóòtú Ìjọba Senegal Sonko di adarí ilé aṣòfin lẹ́yìn tí Ààrẹ Faye yọ ọ́ nípò
26 Èbibi 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Oluwo wù òkú àwọn ọba tí wọ́n sin sí ààfin Iwo kúrò, táwọn ọmọ ọba fi wọ ọ́ lọ sílé ẹjọ́? Àlàyé rèé
26 Èbibi 2026
Ẹ fura o, ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ Boko Haram àti ISWAP ń pète ìkọlù lásìkò ọdún Iléyá - Iléeṣẹ́ ológun ké gbàjarè
26 Èbibi 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Mo ṣetán láti dupò ààrẹ ní 2027, ọ̀sẹ̀ tó ń bọ̀ ni ìdìbò abẹ́lé wa- Omoyele Sowore
23 Èbibi 2026
Ta ni Joel Adesiyan, olùkọ́ táwọn agbébọn pa l'Ogbomoso, àti pé, ṣé òun ni wọ́n pa ní àhámọ́ àwọn ajínigbé?
23 Èbibi 2026
Ẹ wo àwọn olùdíje tó wọlé àtàwọn tó lulẹ̀ nínú ìbò abẹ́nú APC sípò Gómìnà láwọn ìpínlẹ̀
22 Èbibi 2026
Ṣé lóòótọ́ ni pé àwọn ajínigbé tó ṣọṣẹ́ l'Ogbomoso ti ń bá ìjọba Oyo sọ̀rọ̀? Ohun tí a mọ̀ rèé
23 Èbibi 2026
Ṣé òótọ́ ni pé Ààrẹ Tinubu fẹ́ pa orúkọ Naijiria dà tó tún fẹ́ wọ́gilé òfin Sharia ní Naijiria?
22 Èbibi 2026
Obasanjo ṣàlàyé irúfẹ́ àìsàn tó ti ń bá a fínra fún bí ogójì ọdún àti ọ̀nà tó fi ń tọ́jú ara rẹ̀
18 Èbibi 2026
"Agbekoya ní agbára ìbílẹ̀ láti lé àwọn jàndùkú afẹ̀míṣòfò kúrò ní gbogbo ilẹ̀ Yoruba láàrin oṣù kan péré, àmọ́..."
19 Èbibi 2026
Gómìnà Seyi Makinde ní ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣetán láti jíròrò pẹ̀lú àwọn agbébọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ gbé kí wọ́n lè tètè padà wálé
19 Èbibi 2026
Ọlọ́pàá ṣàlàyé bí àwọn alamí ṣe ran àwọn ajínigbé tó kọlu iléẹ̀kọ́, jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Oyo lọ́wọ́
19 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ṣé lóòótọ́ ni Oluwo wù òkú àwọn ọba tí wọ́n sin sí ààfin Iwo kúrò, táwọn ọmọ ọba fi wọ ọ́ lọ sílé ẹjọ́? Àlàyé rèé
2
Olóòtú Ìjọba Senegal Sonko di adarí ilé aṣòfin lẹ́yìn tí Ààrẹ Faye yọ ọ́ nípò
3
Arafat Day: Wo ohun márùn-ún tí ayájọ́ òní fi lọ́lá jùlọ nínú Islam
4
Ẹ fura o, ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ Boko Haram àti ISWAP ń pète ìkọlù lásìkò ọdún Iléyá - Iléeṣẹ́ ológun ké gbàjarè
5
Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un
6
Ẹ gbaradì! Ó ṣeéṣe kí Ebola padà wọ Naijiria lẹ́yìn tó ti búrẹ́kẹ ní DR Congo àti Uganda – NCDC kìlọ̀
7
"Ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ́sì àti mọ́ṣáláṣí dópin, ìsìn kò gbọdọ̀ ju wákàtí méjì lọ, káwọn ṣọ́ọ̀ṣì tó wà ní ìgbéríkò sì kó wá sáàrin ìlú torí ìkọlù agbébọn"
8
Àlàyé rèé lórí bí àwọn aṣọ́bodè ṣe gba bọ́ọ̀sì tó kún fún aṣọ ológun àti òògùn olóró tówó rẹ̀ tó ₦259.68m l'Ogun
9
Ṣé ọmọ Naijiria láṣẹ lábẹ́ òfin láti ya fídíò ọlọ́pàá lẹ́nu iṣẹ́?
10
Ìrọ́ ni pé PDP dara pọ̀ mọ́ APM l‘Oyo, ẹgbẹ́ wa tóbi ju ká dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú kankan lọ, àwa lá borí ìbò ààrẹ - Gbolarumi
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology