BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Wo àwòrán Ọmọọba Harry àti Ìyàwó rẹ̀ nígbà tí wọ́n dé sí Naijiria
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry pẹlu Iyawo rẹ lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Naijiria
Published
11 Èbibi 2024
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n ya fọtọ pẹlu Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan, ti wọn si n ki wọn kaabọ
Àkọlé àwòrán,
Wọn fi ilẹkẹ da Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan lọla lati bu ọwọ fun wọn gẹgẹ bii eeyan nla
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Kanduna, Uba Sani ati Ọmọọba Harry nigba to ba lẹ si ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tun fi aṣọ agbada nla da lọla.
Àkọlé àwòrán,
Awọn onijo ibilẹ fi ijo da Ọmọọba ati iyawo rẹ lara ya lasiko abẹwo.
Àkọlé àwòrán,
Gomina Uba Sani ati Ọmọọba Harry ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry ati Gomina ipinlẹ Kaduna n wo bi awọn onijo ṣe n fi ijo da wọn lara ya ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Awọn onilu ni ile ijọba
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ibilẹ n fi orin da Ọmọọba lọla.
Ṣawari síi
Orilẹede Naijiria
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
02:58
Fídíò,
Ghana must go: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa báàgì yìí àti bó ṣe gbajúmọ̀ ní Naijiria
, Duration2,58
04:47
Fídíò,
"Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́"
, Duration4,47
03:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration3,38
04:06
Fídíò,
Ìwà tí ọ̀pọ̀ ‘Marketer’ ń hù, kù díẹ̀ káà tó, àwọn òṣèré gbà pé wọ́n gbọdọ́ gbéra sílẹ̀ fún wọn láti dìde - Nike Peller
, Duration4,06
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Gbajúgbajà olórin ilẹ̀ Amẹrika, Dolly Parton ti jáde láyé
wákàtí 9 sẹ́yìn
Olubadan sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
25 Ògún 2026
Kí ló dé tí Ọlọ́pàá láti Kwara fẹ́ gbé 'Tani Olohun' ní Ibadan, ṣùgbọ́n tí Sunday Igboho fárígá?
25 Ògún 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Kí ló fa ìró ìbọn tó dún lákọlákọ nígboro Osogbo tí ẹ̀mí kan fi bọ́, báwo ló ṣe kan gómìnà Adeleke àti Davido? Àlàyé rèé
20 Ògún 2026
Ìjàmbá ọkọ̀ ló sọ mí di ẹlẹ́sẹ̀ kan, ìdí eré ìdárayá Onídà ni mo ti ń gbọ́ bùkátà ọmọ méjì - Aanu Kumuyi
20 Ògún 2026
Wo ohun mẹ́jọ pàtàkì nípa ọdún Iṣẹ̀ṣe nílẹ̀ Yorùbá tí ìjọba Oyo, Ogun àti Eko fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́
20 Ògún 2026
Wo gbèdéke owó tí òfin là kalẹ̀ fún olùdíje sípò ààrẹ, gómìnà àtàwọn olùdíje míì láti ná fún ìpolongo ìbò 2027
20 Ògún 2026
"Orí ló kó wa yọ tí APC ò wọlé l'Osun, ọ̀pọ̀ wa kò bá fiṣẹ́ sílẹ̀ ni"- Àwọn òṣìṣẹ́ ìjọba Osun
17 Ògún 2026
Àwọn wo ni ẹbí Adeleke tó dí ètò òṣèlú mú ṣinṣin l'Osun lati ọdun 1979?
17 Ògún 2026
APC Osun sọ̀rọ̀ sókè lórí ìgbésẹ̀ tó kàn lẹ́yìn tó lulẹ̀ nínú ìbò gómìnà
17 Ògún 2026
Kókó ọ̀rọ̀ tí Ẹrọ Arike sọ léyìn tí olùdíje APC lulẹ̀ nínú ètò ìdìbò Gómìnà ìpínlẹ̀ Osun
16 Ògún 2026
Wo ohun tó ṣẹlẹ̀ níbi àyájọ́ ọdún Sango àgbáyé tó wáyé ní ìpínlẹ̀ Oyo
16 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Gbajúgbajà olórin ilẹ̀ Amẹrika, Dolly Parton ti jáde láyé
2
Kí ló dé tí Ọlọ́pàá láti Kwara fẹ́ gbé 'Tani Olohun' ní Ibadan, ṣùgbọ́n tí Sunday Igboho fárígá?
3
Ètò ìsìnkú ti bẹ̀rẹ̀ fún Taiwo Hassan 'Ogogo'
4
Wo àwọn òṣèré tíátà Yoruba méje tó jáde láyé lọ́dún 2026
5
Ọ̀rọ̀ oyè Awùjalẹ̀ tún gbọ̀nà míràn yọ; agboolé Fusengbuwa wọ́ ìjọba ìpínlẹ̀ Ogun àtàwọn Afọbajẹ lọ sílé ẹjọ́
6
Olubadan sọ̀rọ̀ lórí ìròyìn tó ní ó ti darapọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú APC
7
Gbajúgbajà Akéwì asùnjálá ọdẹ, Alabi Ogundepo jade láyé, àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀
8
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ yọwọ́ Makinde kúrò níbi ìfilọ́lẹ̀ òpópónà Ibadan sí Ijebu-Ode? Ohun tí a mọ̀ rèé
9
Kí ló fa ìró ìbọn tó dún lákọlákọ nígboro Osogbo tí ẹ̀mí kan fi bọ́, báwo ló ṣe kan gómìnà Adeleke àti Davido? Àlàyé rèé
10
Àwọn ọlọ́jà ní àwọn kan ló mọ́ọ̀mọ̀ sọná sọ́jà Oranyan ní Ibadan, pè fún ìwádìí látọ̀dọ̀ ìjọ̀ba, Sarafadeen Alli ṣèlérí ìrànwọ́
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology