BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
02:45
Fídíò,
Ìfúpá àwọn èèyàn Ayetoro l‘Ondo ń ga sí, torí bí òkun ṣe ń ya wọ ìlú, gbé iléẹ̀kọ́, ilégbèé, iléeṣẹ́, ilẹ̀ àti ibojì òkù lọ
, Duration2,45
01:26
Fídíò,
Wo àkóbá mọ́kànlá tí ohun mímu ‘Energy Drinks’ le ṣe fún àgọ́ ara rẹ
, Duration1,26
04:32
Fídíò,
Ìjì òjò líle sí òrúlé, da ògiri wó nílé ẹ̀kọ́ girama ọgbọ̀n l‘Ogbomoso, àwọn akẹ́kọ̀ọ́ n kẹ́kọ̀ọ́ lábẹ́ ilé àlàpa
, Duration4,32
02:16
Fídíò,
"Ìjọba rí epo rọ̀bì ní ìlú wa àmọ́ a kò jàǹfààní kankan, kò sí omi, iná, ojú ọ̀nà, ààbò, iléẹ̀kọ́ àti ilé ìwòsàn"
, Duration2,16
03:22
Fídíò,
Àwọn ajínigbé tó kó àwọn akẹ́kọ̀ọ́ yìnbọn sí wa nígbà tí a ń lé wọn wọgbó ìbọn wà kò ràn wọ́n ni – Àwọn ọlọ́dẹ ìlú Esinele
, Duration3,22
02:31
Fídíò,
Wo ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa àrùn Ebola tuntun
, Duration2,31
02:34
Fídíò,
Oronna, jagunjagun tó gbéra láti Oyo lọ tẹ ìlú Ilaro dó
, Duration2,34
02:21
Fídíò,
Olaniyan 'Idamu Industry' Oluwatosin jẹ́wọ́ pé ẹnu nìkan kọ́ lòun ní lórí ètò 'Ṣé o láyà?'
, Duration2,21
05:24
Fídíò,
Agbolé Akọni: Mọ̀ nípa Ogboriefon, akọni tí wọ́n rí he lórí àkìtàn tó di jagunjagun ńlá
, Duration5,24
01:40
Fídíò,
Wo bí hòmóònù ṣe ń mú àyípadà bá ìhùwàsí àwọn obìnrin ní ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀
, Duration1,40
04:05
Fídíò,
Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú - Abayomi Alvin
, Duration4,05
01:02
Fídíò,
Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà
, Duration1,02
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ilé ìgbìmọ̀ àṣofin Ghana buwọ́lu òfin tó kéde ẹ̀wọ̀n ọdún mẹ́ta fún ìbálòpọ̀ akọsákọ àti abosábo
ìṣẹ́jú 18 sẹ́yìn
Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé
wákàtí 3 sẹ́yìn
'A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso,' àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l'Oyo
wákàtí 7 sẹ́yìn
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Télọ̀ kan ju èké fídíò nípa ìkọlù agbébọn l‘Ogun sórí ayélujára láti pawó, ọ̀rọ̀ bá bẹ́yìn yọ fún-un
26 Èbibi 2026
Ìgbésẹ̀ tó dáa ni ikọ̀ Ìrù Ẹkùn ti Sunday Igboho dá sílẹ̀, àmọ́ ìbọn kò gbọdọ̀ di tọ́rọ́ fọ́n kálé láàrin ilú - Onímọ̀ ààbò
25 Èbibi 2026
"Ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ́sì àti mọ́ṣáláṣí dópin, ìsìn kò gbọdọ̀ ju wákàtí méjì lọ, káwọn ṣọ́ọ̀ṣì tó wà ní ìgbéríkò sì kó wá sáàrin ìlú torí ìkọlù agbébọn"
25 Èbibi 2026
Saudi yóò ṣe ògbufọ̀ wáàsí ọjọ́ Arafa Hajj ọdún yìí sí Yorùbá, Hausa àti èdè mẹ́tàlélọ́gbọ̀n míì
22 Èbibi 2026
Afeez Owo ṣàlàyé ohun tó fa ìyapa láàrin òun àti Mide lásìkò kan nínú ìgbéyàwó wọn
21 Èbibi 2026
Ohun tó ṣẹlẹ̀ rèé níbi ìdìbò abẹ́nú APC sípò Gómìnà l'Oyo
21 Èbibi 2026
"Òfin tó mú Eleha ló mú eléégún, ẹ fààyè gbàwọn ẹlẹ́sìn àbáláyé náà láti máa wọ aṣọ ìbílẹ̀ lọ ilé ẹ̀kọ́ ISI n'Ibadan"
21 Èbibi 2026
Sunday Igboho ṣe àfihàn ẹ̀ṣọ́ ààbò "Ija Ekun" tó fẹ́ fi kojú àwọn agbébọn nílẹ̀ Yorùbá bí ìjọba bá fún-un láṣẹ
21 Èbibi 2026
Makinde ṣàgbédìde òfin tó de àwọn fijilanté àtàwọn ẹ̀ṣọ́ ààbò abẹ́nú míì
21 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ọlọ́pàá méjì kú ní ìpínlẹ̀ Osun lẹ́yìn tí ọkọ̀ gbá wọn lójú pópó
2
Báwo ni ayẹyẹ Ojude Oba 2026 ṣe rí láì sí Awujale Ijebu lórí oyè? Ohun tó ṣẹlẹ̀ níbẹ̀ rèé
3
Àlàyé rèé nípa fọ́tò tó ṣàfihàn Ààrẹ Tinubu tó kúnlẹ̀ níta gbangba, tí pásítọ̀ gbọ́wọ́ lé e lórí
4
'A ò lè lọ síbi iṣẹ́ mọ́ torí àwọn olùkọ́ àtàwọn akẹ́kọ̀ọ́ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso,' àwọn olùkọ́ ṣèfẹ̀hónúhàn l'Oyo
5
Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun
6
Ta ló wọlé ìbò abẹ́nú ẹgbẹ́ òṣèlú Accord láti dupò Gómìnà l'Oyo láàrin Oriyomi àti Gudugudu? Ohun tí a mọ̀ rèé
7
"Ẹ jọ̀ọ́ ẹ má jẹ́ kí wọ́n fi ẹ̀mí wa ṣòfò," àwọn olùkọ́ tí agbésùnmọ̀mí jígbé l'Ogbomoso rawọ́ ẹ̀bẹ̀ sí ìjọba
8
Aṣọ oníbúrẹ́dì 500 tí mo wọ lọ síbi àmì ẹ̀yẹ AMVCA dá egbò sí mi lẹ́yìn, mú ẹ̀yìn ro mi, ó jẹ́ kí n fara ṣèṣe - Queen Mercy
9
Iran ṣàlàyé ìdí abájọ tó fi ṣèkọlù sí ibùdó ológun Amẹrika
10
Taa ni Balogun Kuku, bàbá olówó tó mú ẹ̀sìn Islam wọ ilẹ̀ Ijebu, tó tún bẹ̀rẹ̀ ọdún Ojude Ọba?
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology