BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Fo Móríwú kọjá kí o tẹ̀síwájú
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
05:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration5,13
03:37
Fídíò,
Ǹjẹ́ ó tọ́ kí òbí máa kàn án ní dandan f'áwọn ọmọ láti tọ́jú wọn lọ́jọ́ ogbó?
, Duration3,37
05:53
Fídíò,
Ìtàn Balogun Oderinlo tí àjà gbé lọ fún àádọ́rin ọjọ́, ó padà dé pẹ̀lú àpò àbìrà tí ọ̀sanyìn wà, ó di alágbára fún Ibadan
, Duration5,53
02:30
Fídíò,
Wo ọ̀pọ̀ àǹfààní ẹyẹ Igún àti ewu tó wà nínú bí ẹyẹ náà ṣe ń tán lọ nílẹ̀ wa
, Duration2,30
02:54
Fídíò,
Ṣé lóòtọ́ọ́ ni àwọn ẹ̀gbọ́n Ademola Adeleke ti já àkóso ìjọba Osun gbà mọ́ ọ lọ́wọ́? Àlàyé rèé
, Duration2,54
05:26
Fídíò,
Àwọn dókítà ti sọ fún mi pé kí n dẹ́kun sígà fífà àti ọtí mímu-Tope Osoba. Nibo Laye Koju Si?
, Duration5,26
02:30
Fídíò,
Nǹkan kan tí mo mọ̀ ni pé bí orin tí mo bá kọ bá bùkún fún mi, yóò bùkún fún gbogbo èèyàn tó bá gbọ́ ọ - Bisi Manuel
, Duration2,30
03:24
Fídíò,
Àwọn olólùfẹ́ Kola Oyewo sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ lẹ́yìn ìsìnkú rẹ̀
, Duration3,24
04:02
Fídíò,
Àwọn sinimá kan wà tí mo ṣe tí àwọn òbí mi kò lè wò nítorí… - Bolaji Ogunmola, òṣèré tíátà
, Duration4,02
02:58
Fídíò,
Ghana must go: Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa báàgì yìí àti bó ṣe gbajúmọ̀ ní Naijiria
, Duration2,58
04:47
Fídíò,
"Àgọ́ NYSC ni mo ti ń bọ̀, tí mo fi kò ìjàmbá, n kò le dá jókòó, rìn, sùn, yàgbẹ́ tàbí tọ̀, tí mo bá tún ayé wa, n kò ní sìnrú ìlú mọ́"
, Duration4,47
03:38
Fídíò,
À ti tún àwọn ẹ̀rọ̀ BVAS wa ṣe láti dènà kí èèyàn kan lo káàdì ìdìbò ẹlòmíràn nínú ìdìbò gómìna l‘Osun - Alága INEC
, Duration3,38
Ìparí Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ìjọba Niger sọ̀rọ̀ lórí ìgbìyànjú láti dìtẹ̀gbàjọba tó wáyé
wákàtí 6 sẹ́yìn
Wo ìdí mẹ́ta tí akẹ́kọ̀ọ́ tí ilé ẹ̀kọ́ ti gbà wọlè le má rìí orúkọ rẹ̀ lójú òpó JAMB àtàwọn ìgbésẹ̀ tò yẹ kó o gbé
wákàtí 3 sẹ́yìn
Ẹlẹ́mí èṣù làwọn ayálégbé míràn, àfi kí ìjọ̀ba yọwọ́ lọ́rọ́ onílé àti ayálégbé ní Nàìjíríà – Isaac Fayose
29 Ògún 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wo àwọn òṣèré tíátà Yoruba méje tó jáde láyé lọ́dún 2026
25 Ògún 2026
A sa gbogbo ipá wa láti gba ẹ̀mí Ogogo là – Yayi
24 Ògún 2026
Gbajúgbajà Akéwì asùnjálá ọdẹ, Alabi Ogundepo jade láyé, àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀
25 Ògún 2026
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ yọwọ́ Makinde kúrò níbi ìfilọ́lẹ̀ òpópónà Ibadan sí Ijebu-Ode? Ohun tí a mọ̀ rèé
25 Ògún 2026
Òkú sùn, dúkìá ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù bàjẹ́ lásìkò táwọn awakọ̀èrò gbìyànjú láti gba gáréèjì ní Ikire
24 Ògún 2026
Ṣé òótọ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Edo ti fòfin de Davido láti má wọ ìpínlẹ̀ náà mọ́? Gómìnà Okpebholo ṣàlàyé
23 Ògún 2026
Ọwọ́ NDLEA tẹ ìyá àgbà ẹni ọdún 101 tó ń ta oògùn olóró ní ìpínlẹ̀ Ogun
23 Ògún 2026
Wo ìdí tí ìjọba Nàìjíríà fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
24 Ògún 2026
Àkìtàn ya bo ilé ní Guinea, pa èèyàn 31
24 Ògún 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ìjọba Niger sọ̀rọ̀ lórí ìgbìyànjú láti dìtẹ̀gbàjọba tó wáyé
2
Àìsàn jẹjẹrẹ kọlu àgbà òṣèrè mííràn
3
Ọbalayé tó kéré jùlọ lágbáyé jáde láyé lẹ́ni ọdún 34
4
Wo ìdí mẹ́ta tí akẹ́kọ̀ọ́ tí ilé ẹ̀kọ́ ti gbà wọlè le má rìí orúkọ rẹ̀ lójú òpó JAMB àtàwọn ìgbésẹ̀ tò yẹ kó o gbé
5
Wo ọ̀nà àrékérekè tuntun táwọn agbésùnmọ̀mí ń gbà r'owó ní Naijiria bàyìí yàtọ̀ sí gbígba owó ìtúsílẹ̀
6
Ṣé lóòótọ́ ni Kira, ọmọ Ogogo bímọ tuntun? Mọ̀lẹ́bí Ogogo sọ̀rọ̀ síta
7
Wo oúnjẹ méjìlá tó ń ran iṣẹ́ ọpọlọ àti ìròrí lọ́wọ́
8
Èèyà mẹ́ta farapa níbi tí ọlọ́pàá ti yìnbọn pa awakọ̀ lásìkò àyẹ̀wò
9
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
10
Àwọn mọ̀lẹ́bí àwọn tó kú níbí ìkọlù Ikire n bèèrè fín ìdájọ́ òdodo
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology