BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ifiyajẹni
"Abuja ni ọmọ mi ní òun ti ń ṣiṣẹ́, kìí ṣe oníjọ̀ngbọ̀n, àhésọ̀ ọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ kò yé mi tí ọlọ́pàá ṣe ba irin ara ògiri àti ìlẹ̀kùn ilé jẹ́ láti fi tipá wọlé"
8 Agẹmo 2026
Ọmọ Naijiria méjì kú sọ́wọ́ ọlọ́pàá àti lásìkò ìkọlù ní South Africa, ìjọba àpapọ̀ fọnmú, bẹ̀rẹ̀ ìwádìí
8 Agẹmo 2026
Kí ni àyájọ́ 7-7 túmọ̀ sí àti itú tàwọn ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn le pa láti sàmì àyájọ́ náà
7 Agẹmo 2026
4:20
Fídíò,
Oyún ọmọ mi kejì kò tíì pé oṣù mẹ́ta, tí mo fi kan ìdààmú nínú ìgbéyàwó, mo sun ṣégè ẹkún - Wasila Coded
, Duration 4,20
7 Agẹmo 2026
Ọkùnrin kan kú lẹ́yìn Eégún n‘Ibadan, Atọ́kùn eégún, Asòlẹ̀kẹ̀, kó sí gbaga ọlọ́páá báwọn ọmọ ẹ̀yìn eégún ṣe sálọ
6 Agẹmo 2026
9:37
Fídíò,
"Búrẹ́dì ni ọkọ mi lọ rà fún àkọ́bí wa, tí wọ́n fi ṣá a pa ní ọ̀sẹ̀ kan lẹ́yìn ìkómọ ọmọ wa kejì"
, Duration 9,37
23 Òkùdu 2026
Àlàyé lórí báwọn ọ̀dọ́ kan ṣe fi ipá mú abílékọ jáde ní àhámọ́ ọlọ́pàá tí wọ́n sì dáná sun ún
23 Òkùdu 2026
Ìtàgé tó jìn mọ́ Gómìnà Adeleke àtàwọn ikọ̀ rẹ̀ lẹ́sẹ̀ níbi ìpolongo ìbò l'Osun, ohun tí a mọ̀ rèé
11 Òkùdu 2026
Mò sunkún lórí àwọn ọmọ tí wọ́n jí gbé l'Ogbomoso, mi ò mọ̀ pé tèmi náà yóò ṣẹlẹ̀ sí mi - Iya Adelabu
8 Òkùdu 2026
Ìtàn mánigbàgbé: Bí ilà kíkọ ṣe bẹ̀rẹ̀ nílẹ̀ Yorùbá àti bí wọn ṣe fi ilà kíkọ kó ìlú kan lógun
29 Èbibi 2026
Ọwọ́ ọlọ́pàá tẹ akẹ́kọ̀ọ́ mẹ́jọ lórí ẹ̀sùn pé wọ́n dáná sun ilé ẹkọ̀ tí akẹgbẹ́ wọn 16 ti kú
28 Èbibi 2026
Ọ̀pọ̀ èrò n‘Ibadan fẹ̀sùn ajínigbé kan Dókítà kan, wọ́n fẹ́ lú ú pa, dáná sun ọkọ̀ rẹ̀, ọ̀pẹ́ ọlọ́pàá tó dé sásìkò
13 Èbibi 2026
Olùkọ́ fásítì tí wọ́n lù, yẹ̀yẹ́ níta gbangba pé ó ń bá akẹ́kọ̀ọ́ lòpọ̀ ní yàrá ìkàwé, ohun tí a mọ̀ rèé
13 Èbibi 2026
Àlàyé rèé lórí ohun fà á táwọn òṣìṣẹ́ tó ń pèsè omi àti ètò ọ̀gbìn ṣe gunle ìyánṣẹ́lódì
11 Èbibi 2026
"Ń ṣe ni inú mi máa ń bàjẹ́, tí mo bá rántí pé ọmọ ìyá mi ló da ásíìdì sí èmi àti ìyàwó mi lára, tí àwọ̀ ara mi fi bàjẹ́"
4 Ìgbé 2026
Gbas-gbos ní ìpínlẹ̀ Rivers àti àtunbọ̀tán òṣèlú bàbá ìsàlẹ̀ nínú òṣèlú Nàìjíríà
12 Sẹ́rẹ́ 2026
Ìtàn rèé nípa bí ikú Bola Ige ṣe ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn ọdún 24 tó jáde láyé, láì mú ẹni tó pa á
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
5:37
Fídíò,
"Àwọn dókítà yọ kíndìnrín mi láì sọ fún mi, oṣù kẹta rèé tí mi ò lè tọ̀, ṣe ni inú mi ń wú tí mo bá jẹun kékeré"
, Duration 5,37
23 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
Olórí ọ̀dọ́, Afọbajẹ àti ẹgbẹ́ obìnrin ní Epe Ekiti ṣàlàyé ìwà ẹ̀gbin tí ọba hù, tí wọ́n ṣe lé e kúrò nínú ìlú
13 Ọ̀pẹ̀̀ 2025
7:11
Fídíò,
Kí ló fà á táwọn agbébọn ṣe rọgba yí ìpínlẹ̀ Kwara ká àti ipa tó ní lórí aráàlú?
, Duration 7,11
28 Bélú 2025
Olúgbohùn ni wọ́n fi bá ìyàwó mi sọ̀rọ̀, wọ́n ti ra á níyè kó tó tẹ̀lé wọn, kìí ṣe ojú lásán - Ọkọ òṣìsẹ́ FRSC tí wọn pa òun àti ọmọ rẹ̀ ṣàlàyé
25 Bélú 2025
3:47
Fídíò,
"Mo ní ìjàmbá ọkọ̀ lẹ́nu iṣẹ́ ọlọ́pàá, n kò le rìn mọ́, mo ná N25m ẹ̀yáwó báńkì lórí àárẹ̀, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá kò yà sí mi, ìran mi kò lè ṣe iṣẹ́ ọlọ́pàá mọ́"
, Duration 3,47
28 Ọ̀wàrà 2025
Ṣọ́jà la ìbọn mọ́ awakọ̀ kan lórí l'Ondo tó fi kú, iléeṣẹ́ ológun ṣàlàyé bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé
18 Ọ̀wàrà 2025
Àlàyé rèé lórí báwọn olólùfẹ́ ẹgbẹ́ agbábọ́ọ̀lù Kano Pillars ṣe na 3SC ní àlùkì lẹ́yìn tí wọn gbá ọ̀mì ní Kano
13 Ọ̀wàrà 2025
Page
1
nínú
14
1
2
3
4
5
6
7
14
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology